Saturday, June 20, 2026

Ìjọ Aposteli Kristi
Nàìjíríà Àti Òkè Òkun

ILÉ Ẹ̀KỌ́ ỌJỌ́ ÌSINMI

Akori Gbooro:
BÍBÉLÌ NÁÀ: ỌRỌ/ÌṢẸ ỌLỌ́RUN SI ÈNÌYÀN

Oṣù Kínní si oṣù Kejila 2026

Isọri III:
Àwọn Májẹ̀mú Ọlọ́run Àti Igbe Ayé Nínú Májẹ̀mú Láéláé 

June 21, 2026 

Ẹ̀KỌ́ 22

Akori:
Majẹmu Dafidi

Akọsórí:
Emi ti ba ayanfẹ mi da majẹmu, Emi ti bura fun Dafidi, ìránṣẹ́ Mi, iru ọmọ rẹ ni Emi o gbe kalẹ laelae, Emi o si maa gbe itẹ rẹ ro lati irandiran (Orin Dafidi 89:3,4).

Ọlọ́run ṣèlérí nipa itẹ Dafidi lati wa laelae, majẹmu titi aye fun irandiran, ogun-ini ti ìgbàgbọ́ ati ileri

ÀLÀYÉ KÚKÚRÚ 
Ninu Saamu yii, Onisaaamu yii n ronu nipa ìṣàkóso Ọlọ́run to ga julọ lori ohun gbogbo, o si n ran wa leti pe ko si ohun ti o N le ṣẹlẹ̀ laisi ìfẹ́ Rẹ̀. Bakan naa ni o tun n yọ si ileri Ọlọ́run fun Dafidi, ti o si sọ fun un pe iru ọmọ rẹ ni yoo maa jokoo lori itẹ naa nigba gbogbo. Nigba ti ileri yii bẹ̀rẹ̀ pẹlu ila Dafidi, ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìtumọ̀ rẹ jẹyọ níkẹyìn ninu ijọba Kristi, ti o wa lati inu idile Dafidi. Dafidi, Oluṣọ aguntan to nirẹlẹ, jẹ ẹni bi ọkan Ọlọ́run. O dari Israẹli pẹ̀lú iwa ododo ati òtítọ́ inu, ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si majẹmu Rẹ.

Ileri yii si Dafidi n ran wa leti pe Bibeli ki iṣe akojọpọ awọn itan kan lasan-ọrọ/iṣe Ọlọ́run ni si wa. On ṣe afihan abuda aiyipada ti Ọlọrun fun wa, pẹlu iṣotitọ Rẹ ati awọn ìlérí ti On pamọ ni gbogbo irandiran. Nigba ti a ba n ro nipa eyi, a n gba wa niyanju lati ni ìgbẹ́kẹ̀lé ninu, awọn ileri Ọlọ́run ti n pa majẹmu mọ, Ẹni ti O ni eto rere fun ayé wa, gẹgẹ bi O ti ṣe fun Dafidi.

AṢARO LATI INU BÍBÉLÌ 

Mon. 15: OLUWA Fi Ami Ororo Yan Dafidi (O. D. 89:19-21)

Tue. 16: OLUWA Fun Dafidi Ni Ìṣẹgun (O. D. 89:22-23)

Wed. 17; OLUWA Fi Oore-Ọfẹ Han Fun Un (O. D. 89: 24-25)

Thur. 18: Majẹmu OLUWA Duro Pẹlu Dafidi (O. D. 89:26-29).

Fri. 19: Majẹmu Naa Tan De Ori Awọn Ọmọ Rẹ (O. D. 89: 30-32).

Sat. 20: OLUWA Ko Ni Mu Iṣeun Ifẹ Rẹ Kuro (O. D. 89:33)

ÀṢÀRÒ FUN ÌFỌKÀNSÌN 

1. Majẹmu Dafidi nṣafihan iṣeun ati iṣotitọ Ọlọ́run si awọn ti wọn și jẹ olootọ ati olufaraji si I.

2. Nigba ti a ba n gbe igbe aye títọ pẹlu ìṣẹ́ iriju ati awọn amuyẹ ìṣàkóso tòótọ́, Ọlọ́run jẹ́ olootọ lati ṣagbekalẹ májẹ̀mú Rẹ ati lati mu un ṣẹ pẹ̀lú wa.

ẸSẸ BIBELI FUN IPILẸ Ẹ̀KỌ́: 1Kronika 17:11-14

ILEPA ATI ÀWỌN ERONGBA

ILEPA: Lati sọ asoye nipa májẹ̀mú Ọlọ́run pẹlu Dafidi ti n ṣafihan Rẹ gẹgẹ bi Ọlọ́run majẹmu ati Olupa májẹ̀mú mọ.

ÀWỌN ERONGBA: Ni opin ẹ̀kọ́ yii, awọn akẹ́kọ̀ọ́ gbọ́dọ̀ le:

i. ṣàlàyé ohun ti majẹmu Dafidi jẹ;

ii. ṣafihan Ọlọ́run gẹgẹ bi Ọlọ́run ti n pa májẹ̀mú mọ ti O si jẹ olootọ; ati

iii. tọkasi awọn ọna lati wọnu májẹ̀mú ibaṣepo titi aye pẹlu Ọlọ́run. 

IFAARA

ORISUN Ẹ̀KỌ́: 2 SAMUELI 7:5-12; ORIN DAFIDI 89:3-4, 34-37; 132:11-12; ISE 2:22SWJ.
Ogo ni fun Ọlọ́run fun awọn ẹkọ ti O ti kọ wa ni awọn ọ̀sẹ̀ to ti kọjá lọ. Ni ọsẹ to kọjá yii, a wo: Ìjọba Israeli, nibi ti a ti kẹ́kọ̀ọ́ nipa iṣejọba awọn ọba Israeli ati agbekalẹ Ìjọba naa.

Ni ọsẹ yii, a o wo: Majẹmu Dafidi, eyi ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si awọn ìlérí Rẹ lati irandiran. A o ri bi Ọlọ́run ti ṣèlérí fun Dafidi pe ìjọba rẹ yoo maa wa titi nípasẹ̀ arọmọdọmọ rẹ, a si fi ìdánilójú diduro tiiri ati itẹsiwaju rẹ mulẹ. Majẹmu Laelae yii n tọkasi iṣotitọ ati ifaraji Ọlọ́run ti ki i yẹ si mimu awọn ileri Rẹ ṣẹ fun awọn ti wọn ba ṣi jẹ olootọ si I laiyẹsẹ.

Bi oni ti jẹ ọjọ awọn Baba ti ọdun 2026, a n ran wa leti nipa bi Ọlọ́run, Baba wa ọ̀run, ti jẹ olootọ nigba gbogbo ni titọju wa. Ẹ jẹ ki a kọ lati gbe ibaṣepọ to le koko pẹ̀lú Rẹ ro, ẹni ti yoo ba fi ogun ini titi lae silẹ fun awọn iran ọjọ ọla. A o bukun fun wa ni orúkọ Jesu. Amin.

KOKO EKO
I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸLU DÁFÍDÌ 

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DÁFÍDÌ 

ITUPALẸ Ẹ̀KỌ́ 

I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸ̀LÚ DAFIDI (2 Sam. 7:5-12; O. D. 89:3,4).

Nigba ti ọjọ rẹ ba pe, ti ìwọ o si sun pẹ̀lú awọn baba rẹ, Emi o si gbe iru ọmọ rẹ leke lẹ́yìn rẹ, eyi ti o ti inu rẹ jade wa, Emi o si fi idi ìjọba rẹ kalẹ (2 Sam. 7:12).

a. Ọlọ́run, ninu titobi ọlanla Rẹ jẹ Oluṣagbekalẹ májẹ̀mú ati Olùpa majẹmu mọ. Pẹlu pe O jẹ Aiku, O finnufindọ wọnu idipọ/àdéhùn pẹlu eniyan ti i ṣe ẹni kiku ati alaipe.

b. Ni Heberu, "beriyth" n tọkasi àdéhùn laarin ẹgbẹ́(ẹni) meji, nibi ti ẹgbẹ́ (ẹni) kọọkan ti ni lati faraji si pipa awọn ìlérí ti wọn ṣe mọ.

d. Òye niti majẹmu pẹ̀lú Ọlọ́run jẹ́ aarin gbungbun ninu Bibeli, o sin ṣafihan abuda ara ọtọ Rẹ. A gbọ́dọ̀ ni ilepa lati maa ṣafarawe abuda Ọlọ́run yii ninu aye ti wa naa

e. 2 Sam. 7:5-17: Ọlọ́run dá majẹmu ti ko ni tori ninu pẹlu Dafidi, yàtọ̀ si majẹmu Rẹ pẹlu Noa, Abrahamu ati Israẹli.

ẹ. O. D 89:3-4: Ọlọ́run ṣèlérí lati ṣagbekalẹ iru ọmọ Dafidi O si gbe itẹ rẹ ro titi laelae (1 Kron. 22:9-10; 28:5-6). Iru Ọlọ́run olotitọ wo ni a n sin yii!

f. Lati ni iriri majẹmu Ọlọ́run nitootọ, a gbọ́dọ̀ mu ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Rẹ ni pataki julọ, ki a gbe ibaṣepọ titi aye ro pẹlu Rẹ ki awọn ileri Rẹ le wa si ìmúṣẹ ninu aye wa. Ìṣẹ́ isin wa tootọ si Ọlọ́run yoo fi ipa rere lélẹ̀ eyi ti yoo maa fọhun síbẹ̀ lẹyin ti a ba lọ tan.

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DAFIDI (O. D. 89: 34-37; 132:11-12; Işe 2:22swj).

Nitori ti iṣe wolii, ati bi o ti mọ pe, Ọlọ́run ti fi ibura ṣe ileri fun un pe, Ninu iru ọmọ inu rẹ, oun o mu ọkan ìjókòó lori itẹ rẹ (Iṣe. 2:30)

a. O. D. 89:34: Ọlọ́run, Oludamajẹmu ati Olupa majẹmu mọ jẹ olootọ si awọn ileri Rẹ nigba gbogbo (Ìṣe 2:29-37). Eyi mu ki Bibeli ṣe e sinmile ti o si wa titi laelae.

b. Ila 34-37; Ọlọ́run n kiyesi awọn majẹmu Rẹ lati ri i daju pe a ṣe ìmúṣẹ wọn ni pipe. Àwọn ileri Rẹ jẹ ojulowo síbẹ̀, niwọn igba ti a ba ti jẹ olootọ si ojúṣe ti wa, bi o tilẹ̀ jẹ́ pe eniyan le kuna (132:11, 12).

d. 132:11-12: O bu ọla fun májẹ̀mú Rẹ pẹlu Dafidi nipa ṣiṣe agbekalẹ ila ìdílé reẹ gẹgẹ bi oluṣejọba Israeli ti o to fun gbogbo iran.

e. Ila 11: Ileri lati mu ila ìdílé Dafidi gẹgẹ bi ọba duro, níkẹyìn n tọkasi ìmúṣẹ ọjọ ọla ti ìṣejọba Mesaya, ti a muṣẹ ninu Kristi Jesu, Ọba awọn ọba (Ifi. 22:5).

ẹ. Ìṣe 2:22swj: Pétérù ṣàlàyé bi ajinde Jesu ti mu asọtẹlẹ Dafidi ṣẹ, pe, agọ̀ ara Mèsáyà ki yoo dibajẹ, eyi n ṣafihan isopọ laarin Dafidi ati Jesu (O. D 16:10).

f. Majẹmu Dafidi n ṣafihan ipa ara ọtọ Dafidi ninu itan Bibeli ati itẹsiwaju laarin Majẹmu Laelae ati Majẹmu Tuntun, ti o yọrisi ọdọ Jesu, Iru ọmọ Dafidi ti a ti ṣèlérí naa (Lk. 1:32).

AWỌN Ẹ̀KỌ́ TI A RI KỌ

1. Majẹmu Dafidi n ru awọn onigbagbọ sókè lati maa bọlá fun Ọlọ́run ki wọn si maa gbe ogun ini titi laelae ro.

2. Iṣotitọ Ọlọ́run n fun wa ni ẹmi irẹlẹ, o n ru wa sókè lati mọ títóbi julọ ìjọba Rẹ ati lati dagba nipa tẹmi.

ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

1. Ṣalaye iṣotitọ Ọlọ́run ati títóbi julọ Rẹ ninu majẹmu Dafidi. Awọn ẹkọ wo ni a le kọ lara eyi lonii?

2. Bawo ni awọn onigbagbọ ninu Kristi ṣe le mu majẹmu Ọlọ́run dúró lode lonii?

ÌDÁHÙN TI A DABAA FUN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

ÌDÁHÙN SI ÌBÉÈRÈ 1

* Ọlọ́run ninu titobi julọ Rẹ, yan Dafidi gẹ́gẹ́ bi ẹni ami ororo Rẹ O si da majẹmu àìnípẹ̀kun lati fidi ìjọba rẹ múlẹ̀. 

* Majẹmu yii ṣan wọnu majẹmu ti Mèsáyà pẹlu awọn ènìyàn Ọlọ́run. 

* Dafidi ò gba majẹmu yii nípasẹ̀ iwa òdodo rẹ; ìyàn Ọlọ́run, ti o da lori oore-ọfẹ Rẹ ni, kii ṣe mímọ-ọn-ṣe Dafidi.

* Ninu iṣotitọ Rẹ, Ọlọ́run ri i dájú pé majẹmu yii di mimúṣẹ (O. D. 89:34).

* Dafidi ko ipa pataki nipa gbigbe ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Ọlọ́run ro, ní bí o ti ṣàkóso pẹlu òtítọ́ inu, ọkan olùsọ-àgùntàn, ati iwa irẹlẹ to jinlẹ.

* Awon eko fun wa lonii:

        * Awọn obi gbọ́dọ̀ ko/gbe ogun ini oniwa-bi-Ọlọrun ro fun awọn ọmọ wọn.

        * Eyi n yanana pàtàkì ogun ini ìdílé ati ipa rẹ lori awọn iran ọjọ́ ọla.

IDAHUN SI IBEERE 2
A le pa majẹmu Ọlọ́run mọ laaye ninu aye wa lonii nipa:

i. Gbígbé ibaṣepọ to kun fun Ẹ̀mi ti o si le koko ro pẹlu Ọlọ́run;

ii. Ṣiṣe agbekalẹ akoko ìfọkànsìn ti ìdílé lojoojumọ;

iii. Kíkọ ìdílé rẹ ni awọn ẹkọ ati ilana Bibeli to ṣe iyebiye;

iv. Fifaaye gba Jesu lati dari ati lati maa tọ idile rẹ;

v. Fifi Jésù han ìdílé/ẹbi rẹ - Oun ni ẹ̀bùn ti o tobi julọ;

vi. Fifun Ọlọ́run ni ìjọsìn tòótọ́ ati eyi to ṣe itẹwọgba;

vii. Jijẹ ẹni to n kopa to si n ṣe deede ninu ìṣẹ́ isin Ọlọ́run pẹ̀lú awọn ọmọ rẹ;

viii. Ṣiṣatilẹyin ìṣe Ọlọ́run ninu ijọ ti o n lọ; ati

ix. Riri isẹra ẹni/ibawi gẹ́gẹ́ bi ami ifẹ Ọlọ́run ati ipongbẹ Rẹ lati ṣe odiwọn wa sinu àwòrán Rẹ.

ÀMÚLÒ FUN IGBE AYE ẸNI 

Ọlọ́run ni eto ara-ọ̀tọ̀ fun olukuluku wa, gẹgẹ bi O ti ni in fun eyi si bẹ̀rẹ̀ pẹlu gbígbẹkẹle E ati titẹle awọn àṣẹ Rẹ. A le ma fi igba gbogbo ni ẹkunrẹrẹ oye eto Rẹ, ṣugbọn a le ni ìdánilójú pe ọna Rẹ tayọ ohunkohun ti a le finuro. Ẹ jẹ ki a kọjú wasi gbigbe igbe aye to n bu ọlá fun Ọlọ́run ki a si kó ogun ini ti n ṣafihan ìfẹ́ ati iṣotitọ Rẹ. Gẹgẹ bi baba to mọ ikẹ ati igẹ ti maa n tọju awọn ọmọ rẹ, Ọlọ́run wa fun wa nigba gbogbo, On tọ wa pẹlu itọju ìfẹ́ Rẹ̀. Ẹ jẹ ki a maa gbe ayé wa ni ọna to ba ifẹ Rẹ mu, ki a gbẹkẹle E lati dari wa si ọjọ́ ọ̀la ti O ti ṣètò fun wa.

IGUNLẸ 
Eyi ni igunlẹ Ẹ̀kọ 22. A gba wa níyànjú lati faramọ majẹmu Ọlọ́run, ati gẹgẹ bi obi, oluṣo-aguntan ati olutọnisọna, a gbọ́dọ̀ lakaka lati gbe ogun ini oníwà-bí-Ọlọ́run ti yoo wa laelae ró, gẹgẹ bi ti majẹmu Dafidi. Awọn obi gbọ́dọ̀ maa gbadura fun ọjọ́ ọ̀la awọn ọmọ wọn, ki wọn maa ṣàfẹ́rí ìtọ́ni ati ìbùkún Ọlọ́run fun wọn.

ÀkíyèsíÌjọ Aposteli Kristi
Nàìjíríà Àti Òkè Òkun

ILÉ Ẹ̀KỌ́ ỌJỌ́ ÌSINMI

Akori Gbooro:
BÍBÉLÌ NÁÀ: ỌRỌ/ÌṢẸ ỌLỌ́RUN SI ÈNÌYÀN

Oṣù Kínní si oṣù Kejila 2026

Isọri III:
Àwọn Májẹ̀mú Ọlọ́run Àti Igbe Ayé Nínú Májẹ̀mú Láéláé 

June 21, 2026 

Ẹ̀KỌ́ 22

Akori:
Majẹmu Dafidi

Akọsórí:
Emi ti ba ayanfẹ mi da majẹmu, Emi ti bura fun Dafidi, ìránṣẹ́ Mi, iru ọmọ rẹ ni Emi o gbe kalẹ laelae, Emi o si maa gbe itẹ rẹ ro lati irandiran (Orin Dafidi 89:3,4).

Ọlọ́run ṣèlérí nipa itẹ Dafidi lati wa laelae, majẹmu titi aye fun irandiran, ogun-ini ti ìgbàgbọ́ ati ileri

ÀLÀYÉ KÚKÚRÚ 
Ninu Saamu yii, Onisaaamu yii n ronu nipa ìṣàkóso Ọlọ́run to ga julọ lori ohun gbogbo, o si n ran wa leti pe ko si ohun ti o N le ṣẹlẹ̀ laisi ìfẹ́ Rẹ̀. Bakan naa ni o tun n yọ si ileri Ọlọ́run fun Dafidi, ti o si sọ fun un pe iru ọmọ rẹ ni yoo maa jokoo lori itẹ naa nigba gbogbo. Nigba ti ileri yii bẹ̀rẹ̀ pẹlu ila Dafidi, ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìtumọ̀ rẹ jẹyọ níkẹyìn ninu ijọba Kristi, ti o wa lati inu idile Dafidi. Dafidi, Oluṣọ aguntan to nirẹlẹ, jẹ ẹni bi ọkan Ọlọ́run. O dari Israẹli pẹ̀lú iwa ododo ati òtítọ́ inu, ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si majẹmu Rẹ.

Ileri yii si Dafidi n ran wa leti pe Bibeli ki iṣe akojọpọ awọn itan kan lasan-ọrọ/iṣe Ọlọ́run ni si wa. On ṣe afihan abuda aiyipada ti Ọlọrun fun wa, pẹlu iṣotitọ Rẹ ati awọn ìlérí ti On pamọ ni gbogbo irandiran. Nigba ti a ba n ro nipa eyi, a n gba wa niyanju lati ni ìgbẹ́kẹ̀lé ninu, awọn ileri Ọlọ́run ti n pa majẹmu mọ, Ẹni ti O ni eto rere fun ayé wa, gẹgẹ bi O ti ṣe fun Dafidi.

AṢARO LATI INU BÍBÉLÌ 

Mon. 15: OLUWA Fi Ami Ororo Yan Dafidi (O. D. 89:19-21)

Tue. 16: OLUWA Fun Dafidi Ni Ìṣẹgun (O. D. 89:22-23)

Wed. 17; OLUWA Fi Oore-Ọfẹ Han Fun Un (O. D. 89: 24-25)

Thur. 18: Majẹmu OLUWA Duro Pẹlu Dafidi (O. D. 89:26-29).

Fri. 19: Majẹmu Naa Tan De Ori Awọn Ọmọ Rẹ (O. D. 89: 30-32).

Sat. 20: OLUWA Ko Ni Mu Iṣeun Ifẹ Rẹ Kuro (O. D. 89:33)

ÀṢÀRÒ FUN ÌFỌKÀNSÌN 

1. Majẹmu Dafidi nṣafihan iṣeun ati iṣotitọ Ọlọ́run si awọn ti wọn și jẹ olootọ ati olufaraji si I.

2. Nigba ti a ba n gbe igbe aye títọ pẹlu ìṣẹ́ iriju ati awọn amuyẹ ìṣàkóso tòótọ́, Ọlọ́run jẹ́ olootọ lati ṣagbekalẹ májẹ̀mú Rẹ ati lati mu un ṣẹ pẹ̀lú wa.

ẸSẸ BIBELI FUN IPILẸ Ẹ̀KỌ́: 1Kronika 17:11-14

ILEPA ATI ÀWỌN ERONGBA

ILEPA: Lati sọ asoye nipa májẹ̀mú Ọlọ́run pẹlu Dafidi ti n ṣafihan Rẹ gẹgẹ bi Ọlọ́run majẹmu ati Olupa májẹ̀mú mọ.

ÀWỌN ERONGBA: Ni opin ẹ̀kọ́ yii, awọn akẹ́kọ̀ọ́ gbọ́dọ̀ le:

i. ṣàlàyé ohun ti majẹmu Dafidi jẹ;

ii. ṣafihan Ọlọ́run gẹgẹ bi Ọlọ́run ti n pa májẹ̀mú mọ ti O si jẹ olootọ; ati

iii. tọkasi awọn ọna lati wọnu májẹ̀mú ibaṣepo titi aye pẹlu Ọlọ́run. 

IFAARA

ORISUN Ẹ̀KỌ́: 2 SAMUELI 7:5-12; ORIN DAFIDI 89:3-4, 34-37; 132:11-12; ISE 2:22SWJ.
Ogo ni fun Ọlọ́run fun awọn ẹkọ ti O ti kọ wa ni awọn ọ̀sẹ̀ to ti kọjá lọ. Ni ọsẹ to kọjá yii, a wo: Ìjọba Israeli, nibi ti a ti kẹ́kọ̀ọ́ nipa iṣejọba awọn ọba Israeli ati agbekalẹ Ìjọba naa.

Ni ọsẹ yii, a o wo: Majẹmu Dafidi, eyi ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si awọn ìlérí Rẹ lati irandiran. A o ri bi Ọlọ́run ti ṣèlérí fun Dafidi pe ìjọba rẹ yoo maa wa titi nípasẹ̀ arọmọdọmọ rẹ, a si fi ìdánilójú diduro tiiri ati itẹsiwaju rẹ mulẹ. Majẹmu Laelae yii n tọkasi iṣotitọ ati ifaraji Ọlọ́run ti ki i yẹ si mimu awọn ileri Rẹ ṣẹ fun awọn ti wọn ba ṣi jẹ olootọ si I laiyẹsẹ.

Bi oni ti jẹ ọjọ awọn Baba ti ọdun 2026, a n ran wa leti nipa bi Ọlọ́run, Baba wa ọ̀run, ti jẹ olootọ nigba gbogbo ni titọju wa. Ẹ jẹ ki a kọ lati gbe ibaṣepọ to le koko pẹ̀lú Rẹ ro, ẹni ti yoo ba fi ogun ini titi lae silẹ fun awọn iran ọjọ ọla. A o bukun fun wa ni orúkọ Jesu. Amin.

KOKO EKO
I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸLU DÁFÍDÌ 

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DÁFÍDÌ 

ITUPALẸ Ẹ̀KỌ́ 

I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸ̀LÚ DAFIDI (2 Sam. 7:5-12; O. D. 89:3,4).

Nigba ti ọjọ rẹ ba pe, ti ìwọ o si sun pẹ̀lú awọn baba rẹ, Emi o si gbe iru ọmọ rẹ leke lẹ́yìn rẹ, eyi ti o ti inu rẹ jade wa, Emi o si fi idi ìjọba rẹ kalẹ (2 Sam. 7:12).

a. Ọlọ́run, ninu titobi ọlanla Rẹ jẹ Oluṣagbekalẹ májẹ̀mú ati Olùpa majẹmu mọ. Pẹlu pe O jẹ Aiku, O finnufindọ wọnu idipọ/àdéhùn pẹlu eniyan ti i ṣe ẹni kiku ati alaipe.

b. Ni Heberu, "beriyth" n tọkasi àdéhùn laarin ẹgbẹ́(ẹni) meji, nibi ti ẹgbẹ́ (ẹni) kọọkan ti ni lati faraji si pipa awọn ìlérí ti wọn ṣe mọ.

d. Òye niti majẹmu pẹ̀lú Ọlọ́run jẹ́ aarin gbungbun ninu Bibeli, o sin ṣafihan abuda ara ọtọ Rẹ. A gbọ́dọ̀ ni ilepa lati maa ṣafarawe abuda Ọlọ́run yii ninu aye ti wa naa

e. 2 Sam. 7:5-17: Ọlọ́run dá majẹmu ti ko ni tori ninu pẹlu Dafidi, yàtọ̀ si majẹmu Rẹ pẹlu Noa, Abrahamu ati Israẹli.

ẹ. O. D 89:3-4: Ọlọ́run ṣèlérí lati ṣagbekalẹ iru ọmọ Dafidi O si gbe itẹ rẹ ro titi laelae (1 Kron. 22:9-10; 28:5-6). Iru Ọlọ́run olotitọ wo ni a n sin yii!

f. Lati ni iriri majẹmu Ọlọ́run nitootọ, a gbọ́dọ̀ mu ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Rẹ ni pataki julọ, ki a gbe ibaṣepọ titi aye ro pẹlu Rẹ ki awọn ileri Rẹ le wa si ìmúṣẹ ninu aye wa. Ìṣẹ́ isin wa tootọ si Ọlọ́run yoo fi ipa rere lélẹ̀ eyi ti yoo maa fọhun síbẹ̀ lẹyin ti a ba lọ tan.

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DAFIDI (O. D. 89: 34-37; 132:11-12; Işe 2:22swj).

Nitori ti iṣe wolii, ati bi o ti mọ pe, Ọlọ́run ti fi ibura ṣe ileri fun un pe, Ninu iru ọmọ inu rẹ, oun o mu ọkan ìjókòó lori itẹ rẹ (Iṣe. 2:30)

a. O. D. 89:34: Ọlọ́run, Oludamajẹmu ati Olupa majẹmu mọ jẹ olootọ si awọn ileri Rẹ nigba gbogbo (Ìṣe 2:29-37). Eyi mu ki Bibeli ṣe e sinmile ti o si wa titi laelae.

b. Ila 34-37; Ọlọ́run n kiyesi awọn majẹmu Rẹ lati ri i daju pe a ṣe ìmúṣẹ wọn ni pipe. Àwọn ileri Rẹ jẹ ojulowo síbẹ̀, niwọn igba ti a ba ti jẹ olootọ si ojúṣe ti wa, bi o tilẹ̀ jẹ́ pe eniyan le kuna (132:11, 12).

d. 132:11-12: O bu ọla fun májẹ̀mú Rẹ pẹlu Dafidi nipa ṣiṣe agbekalẹ ila ìdílé reẹ gẹgẹ bi oluṣejọba Israeli ti o to fun gbogbo iran.

e. Ila 11: Ileri lati mu ila ìdílé Dafidi gẹgẹ bi ọba duro, níkẹyìn n tọkasi ìmúṣẹ ọjọ ọla ti ìṣejọba Mesaya, ti a muṣẹ ninu Kristi Jesu, Ọba awọn ọba (Ifi. 22:5).

ẹ. Ìṣe 2:22swj: Pétérù ṣàlàyé bi ajinde Jesu ti mu asọtẹlẹ Dafidi ṣẹ, pe, agọ̀ ara Mèsáyà ki yoo dibajẹ, eyi n ṣafihan isopọ laarin Dafidi ati Jesu (O. D 16:10).

f. Majẹmu Dafidi n ṣafihan ipa ara ọtọ Dafidi ninu itan Bibeli ati itẹsiwaju laarin Majẹmu Laelae ati Majẹmu Tuntun, ti o yọrisi ọdọ Jesu, Iru ọmọ Dafidi ti a ti ṣèlérí naa (Lk. 1:32).

AWỌN Ẹ̀KỌ́ TI A RI KỌ

1. Majẹmu Dafidi n ru awọn onigbagbọ sókè lati maa bọlá fun Ọlọ́run ki wọn si maa gbe ogun ini titi laelae ro.

2. Iṣotitọ Ọlọ́run n fun wa ni ẹmi irẹlẹ, o n ru wa sókè lati mọ títóbi julọ ìjọba Rẹ ati lati dagba nipa tẹmi.

ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

1. Ṣalaye iṣotitọ Ọlọ́run ati títóbi julọ Rẹ ninu majẹmu Dafidi. Awọn ẹkọ wo ni a le kọ lara eyi lonii?

2. Bawo ni awọn onigbagbọ ninu Kristi ṣe le mu majẹmu Ọlọ́run dúró lode lonii?

ÌDÁHÙN TI A DABAA FUN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

ÌDÁHÙN SI ÌBÉÈRÈ 1

* Ọlọ́run ninu titobi julọ Rẹ, yan Dafidi gẹ́gẹ́ bi ẹni ami ororo Rẹ O si da majẹmu àìnípẹ̀kun lati fidi ìjọba rẹ múlẹ̀. 

* Majẹmu yii ṣan wọnu majẹmu ti Mèsáyà pẹlu awọn ènìyàn Ọlọ́run. 

* Dafidi ò gba majẹmu yii nípasẹ̀ iwa òdodo rẹ; ìyàn Ọlọ́run, ti o da lori oore-ọfẹ Rẹ ni, kii ṣe mímọ-ọn-ṣe Dafidi.

* Ninu iṣotitọ Rẹ, Ọlọ́run ri i dájú pé majẹmu yii di mimúṣẹ (O. D. 89:34).

* Dafidi ko ipa pataki nipa gbigbe ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Ọlọ́run ro, ní bí o ti ṣàkóso pẹlu òtítọ́ inu, ọkan olùsọ-àgùntàn, ati iwa irẹlẹ to jinlẹ.

* Awon eko fun wa lonii:

        * Awọn obi gbọ́dọ̀ ko/gbe ogun ini oniwa-bi-Ọlọrun ro fun awọn ọmọ wọn.

        * Eyi n yanana pàtàkì ogun ini ìdílé ati ipa rẹ lori awọn iran ọjọ́ ọla.

IDAHUN SI IBEERE 2
A le pa majẹmu Ọlọ́run mọ laaye ninu aye wa lonii nipa:

i. Gbígbé ibaṣepọ to kun fun Ẹ̀mi ti o si le koko ro pẹlu Ọlọ́run;

ii. Ṣiṣe agbekalẹ akoko ìfọkànsìn ti ìdílé lojoojumọ;

iii. Kíkọ ìdílé rẹ ni awọn ẹkọ ati ilana Bibeli to ṣe iyebiye;

iv. Fifaaye gba Jesu lati dari ati lati maa tọ idile rẹ;

v. Fifi Jésù han ìdílé/ẹbi rẹ - Oun ni ẹ̀bùn ti o tobi julọ;

vi. Fifun Ọlọ́run ni ìjọsìn tòótọ́ ati eyi to ṣe itẹwọgba;

vii. Jijẹ ẹni to n kopa to si n ṣe deede ninu ìṣẹ́ isin Ọlọ́run pẹ̀lú awọn ọmọ rẹ;

viii. Ṣiṣatilẹyin ìṣe Ọlọ́run ninu ijọ ti o n lọ; ati

ix. Riri isẹra ẹni/ibawi gẹ́gẹ́ bi ami ifẹ Ọlọ́run ati ipongbẹ Rẹ lati ṣe odiwọn wa sinu àwòrán Rẹ.

ÀMÚLÒ FUN IGBE AYE ẸNI 

Ọlọ́run ni eto ara-ọ̀tọ̀ fun olukuluku wa, gẹgẹ bi O ti ni in fun eyi si bẹ̀rẹ̀ pẹlu gbígbẹkẹle E ati titẹle awọn àṣẹ Rẹ. A le ma fi igba gbogbo ni ẹkunrẹrẹ oye eto Rẹ, ṣugbọn a le ni ìdánilójú pe ọna Rẹ tayọ ohunkohun ti a le finuro. Ẹ jẹ ki a kọjú wasi gbigbe igbe aye to n bu ọlá fun Ọlọ́run ki a si kó ogun ini ti n ṣafihan ìfẹ́ ati iṣotitọ Rẹ. Gẹgẹ bi baba to mọ ikẹ ati igẹ ti maa n tọju awọn ọmọ rẹ, Ọlọ́run wa fun wa nigba gbogbo, On tọ wa pẹlu itọju ìfẹ́ Rẹ̀. Ẹ jẹ ki a maa gbe ayé wa ni ọna to ba ifẹ Rẹ mu, ki a gbẹkẹle E lati dari wa si ọjọ́ ọ̀la ti O ti ṣètò fun wa.

IGUNLẸ 
Eyi ni igunlẹ Ẹ̀kọ 22. A gba wa níyànjú lati faramọ majẹmu Ọlọ́run, ati gẹgẹ bi obi, oluṣo-aguntan ati olutọnisọna, a gbọ́dọ̀ lakaka lati gbe ogun ini oníwà-bí-Ọlọ́run ti yoo wa laelae ró, gẹgẹ bi ti majẹmu Dafidi. Awọn obi gbọ́dọ̀ maa gbadura fun ọjọ́ ọ̀la awọn ọmọ wọn, ki wọn maa ṣàfẹ́rí ìtọ́ni ati ìbùkún Ọlọ́run fun wọn.

Àkíyèsí

2026 CAC Sunday School Lesson 22

CHRIST APOSTOLIC CHURCH
Nigeria & Overseas

SUNDAY SCHOOL LESSON

Theme:
The BIBLE: God's Message to Man

January - December 2026

Unit III:
God's Covenants And Life In The Old Testament 

June 21, 2026 (Father's Day) 

Lesson 22

Topic:
The Davidic Covenant

Memory Scripture:
I have made a covenant with my chosen, I have sworn to my servant David: Your seed I will establish forever. And build up your throne to all generations (Psalm 89:3,4).

God promises David's throne forever, a lasting covenant for all generations, a legacy of faith and promise.

BRIEF COMMENT

In this Psalm, the psalmist reflects on God's absolute control over everything and reminds us that nothing happens outside His will. It also celebrates God's promise to David, telling him that his descendants would always sit on the throne. While this promise began with David's line, it ultimately finds its fullest meaning in Christ's reign, who comes from David's family. David, a humble shepherd, was a man after God's own heart. He led Israel with honesty and integrity, showing God's faithfulness to His covenant.

This promise to David reminds us that the Bible isn't just a collection of stories-it is God's message to us. It shows us God's unchanging nature, His faithfulness and the promises He keeps across generations. When we reflect on this, we are encouraged to trust in God's promises, follow His guidance and remember that He is a covenant-keeping God Who has a good plan for our lives, just as He did for David.

DEVOTIONAL BIBLE READINGS

Mon. 15: The LORD Anoints David (Ps. 89:19-21)

Tue. 16: The LORD Gives David Victory (Ps. 89: 22-23)

Wed. 17: The LORD Shows Mercy To Him (Ps. 89:24-25)

Thu. 18: The LORD's Covenant Stands With David (Ps. 89:26-29)

Fri. 19: The Covenant Extends To His Sons (Ps. 89:30-32)

Sat. 20: The LORD Wouldn't Remove His Loving-kindness (Ps. 89:33)

DEVOTIONAL THOUGHTS

1. The Davidic covenant shows God's goodness and faithfulness to those who remain loyal and committed to Him.

2. When we live uprightly with true stewardship and leadership qualities, God is faithful to establish and fulfil His covenant with us.

BACKGROUND SCRIPTURE: 1 Chronicles 17:11-14

AIM AND OBJECTIVES

AIM: To clarify God's covenant with David, showing Him as the God of covenants and Keeper of promises.

OBJECTIVE: By the end of this lesson, learners should be able to:

i. explain what the Davidic covenant is;

ii. identify God as a covenant-keeping and faithful God; and

iii. identify ways to enter into lasting covenant relationship with God.

INTRODUCTION

TEXTUAL SOURCES: 2 SAMUEL 7:5-12; PSALMS 89:3-4, 34-37; 132:11-12; АCTS 2:22FF
To God be the glory for the lessons He has taught us in recent weeks. Last week, we explored: The Kingdom of Israel, where we learnt about the reigns of Israel's kings and the establishment of the kingdom.

This week, we focus on: The Davidic Covenant, which reveals God's faithfulness to His promises across generations. We will discover how God promised David that his kingdom would endure through his descendants, ensuring its stability and continuity. This everlasting covenant demonstrates God's unwavering faithfulness and commitment to fulfilling His promises for those who remain faithful to Him.

As today is Father's Day 2026, we are reminded of how God, our Heavenly Father, has always been faithful in caring for us. Let us learn to build a strong relationship with Him, one that will leave a lasting legacy for future generations. May we be blessed in Jesus' name. Amen.

LESSON OUTLINE

I. GOD'S ETERNAL COVENANT WITH DAVID

II. GOD'S FAITHFULNESS TO THE DAVIDIC COVENANT

LESSON EXPOSITION

I. GOD'S ETERNAL COVENANT WITH DAVID (2 Sam. 7:5-12; Ps. 89:3,4)
When your days are fulfilled and you rest with your fathers, I will set up your seed after you, who will come from your body, and I will establish his kingdom (2 Sam. 7:12).

a) God, in His greatness, is both a covenant Maker and Keeper. Despite His immortality, He freely enters into binding agreements with man, who are mortal and imperfect.

b) In Hebrew, beriyth refers to an agreement between two parties, where each commits to keeping promises made.

c) The idea of a covenant with God is central in the Bible and reflects His unique nature. We should aim to mirror this attribute of God in our own lives.

d) 2 Sam. 7:5-17: God made an unconditional covenant with David, separate from His covenants with Noah, Abraham and Israel.

e) Ps. 89:3-4: God promised to establish David's descendants and build his throne forever (1 Chro. 22:9-10; 28:5-6). What a faithful God we serve!

f) To truly experience God's covenant, we must prioritise intimacy with Him, building a lasting relationship so His promises can be fully fulfilled in our lives. Our sincere service to God will leave a legacy that speaks long after we are gone.

II. GOD'S FAITHFULNESS TO DAVIDIC COVENANT (Ps. 89:34-37; 132:11-12; Acts 2:22ff)

Therefore, being a prophet, and knowing that God had sworn with an oath to him that of the fruit of his body, according to the flesh. He would raise up the Christ to sit on his throne (Act 2:30).

a) Ps. 89:34: God, the covenant Maker and Keeper, is always true to His promises (Acts 2:29-37). This makes the Bible reliable and enduring.

b) lines 34-37: God watches over His covenants to ensure they are perfectly fulfilled. His promises remain valid as long as we stay true to our part, though humans may falter (132:11,12).

c) 132:11-12: He honoured His covenant with David by establishing his dynasty as Israel's rightful rulers for all generations.

d) line 11: The promise to sustain David's dynasty ultimately points to the future fulfilment of the Messiah's reign, fulfilled in Christ Jesus, the King of kings (Rev. 22:5).

e) Acts 2:22ff: Peter explains how Jesus' resurrection fulfilled David's prophecy that the Messiah's body would not decay, showing the connection between David and Jesus (Ps. 16:10).

f) The Davidic covenant reveals David's special role in biblical history and the continuity between the Old and New Testaments, leading to Jesus, the promised descendant of David (Lk. 1:32).

LESSONS DERIVED
1. The Davidic covenant encourages believers to honour God and build a lasting legacy.

2. God's faithfulness humbles us, inspiring us to recognise His sovereignty and grow spiritually.

QUESTIONS
1. Explain God's faithfulness and sovereignty in the Davidic covenant. What lessons can we learn from it today?

2. How can believers in Christ sustain God's covenant today?

SUGGESTED ANSWERS TO QUESTIONS

ANSWER TO QUESTION 1
* God, in His sovereignty, chose David as His anointed one and made an everlasting covenant to establish his reign.

* This covenant flows into the Messianic covenant with God's people.

* David didn't earn this covenant through his own righteousness; it was God's choice, based on His grace, not David's merit.

* In His faithfulness, God ensured this covenant would be fulfilled (Ps. 89:34).

* David played a key role by building a close relationship with God, leading with integrity, a shepherd's heart, and deep humility.

* Lessons for us today:
       Parents should build a godly legacy for their children.

      This highlights the importance of family legacy and its impact on future generations.

ANSWER TO QUESTION 2

We can keep God's covenant alive in our lives today by:
i. building a strong, Spirit-filled relationship with God;

ii. setting up a daily family devotional time;

iii. teaching your family biblical values and principles;

iv. allowing Jesus to lead and guide your home;

v. introducing Jesus to your family-He is the greatest gift;

vi. offering sincere and acceptable worship to God;

vii. being active and punctual in God's service with your children; viii.supporting the work of God in your local church; and

ix. viewing discipline as a sign of God's love and His desire to shape us into His image.

LIFE APPLICATION

God has a unique plan for each of us, just just as He had for David. Like David, we are called to walk in God's purpose and this begins with trusting Him and following His commands. We may not always fully understand His plan, but we can be confident that His way is far better than anything we could imagine. Let us focus on living a life that honours God and builds a legacy that shows His love and faithfulness. Just as a caring father looks after his children, God is always there for us, guiding us with His loving care. Let's live in a way that follows His will, trusting Him to lead us into the future He has prepared for us.

CONCLUSION
This concludes Lesson 22. We are encouraged to embrace God's covenant, and as parents, pastors and mentors, we must strive to build godly legacies that will endure, much like the Davidic covenant. Parents should pray for their children's futures, seeking God's guidance and blessings for them.

Note


______________________________________________Ìjọ Aposteli Kristi
Nàìjíríà Àti Òkè Òkun

ILÉ Ẹ̀KỌ́ ỌJỌ́ ÌSINMI

Akori Gbooro:
BÍBÉLÌ NÁÀ: ỌRỌ/ÌṢẸ ỌLỌ́RUN SI ÈNÌYÀN

Oṣù Kínní si oṣù Kejila 2026

Isọri III:
Àwọn Májẹ̀mú Ọlọ́run Àti Igbe Ayé Nínú Májẹ̀mú Láéláé 

June 21, 2026 

Ẹ̀KỌ́ 22

Akori:
Majẹmu Dafidi

Akọsórí:
Emi ti ba ayanfẹ mi da majẹmu, Emi ti bura fun Dafidi, ìránṣẹ́ Mi, iru ọmọ rẹ ni Emi o gbe kalẹ laelae, Emi o si maa gbe itẹ rẹ ro lati irandiran (Orin Dafidi 89:3,4).

Ọlọ́run ṣèlérí nipa itẹ Dafidi lati wa laelae, majẹmu titi aye fun irandiran, ogun-ini ti ìgbàgbọ́ ati ileri

ÀLÀYÉ KÚKÚRÚ 
Ninu Saamu yii, Onisaaamu yii n ronu nipa ìṣàkóso Ọlọ́run to ga julọ lori ohun gbogbo, o si n ran wa leti pe ko si ohun ti o N le ṣẹlẹ̀ laisi ìfẹ́ Rẹ̀. Bakan naa ni o tun n yọ si ileri Ọlọ́run fun Dafidi, ti o si sọ fun un pe iru ọmọ rẹ ni yoo maa jokoo lori itẹ naa nigba gbogbo. Nigba ti ileri yii bẹ̀rẹ̀ pẹlu ila Dafidi, ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìtumọ̀ rẹ jẹyọ níkẹyìn ninu ijọba Kristi, ti o wa lati inu idile Dafidi. Dafidi, Oluṣọ aguntan to nirẹlẹ, jẹ ẹni bi ọkan Ọlọ́run. O dari Israẹli pẹ̀lú iwa ododo ati òtítọ́ inu, ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si majẹmu Rẹ.

Ileri yii si Dafidi n ran wa leti pe Bibeli ki iṣe akojọpọ awọn itan kan lasan-ọrọ/iṣe Ọlọ́run ni si wa. On ṣe afihan abuda aiyipada ti Ọlọrun fun wa, pẹlu iṣotitọ Rẹ ati awọn ìlérí ti On pamọ ni gbogbo irandiran. Nigba ti a ba n ro nipa eyi, a n gba wa niyanju lati ni ìgbẹ́kẹ̀lé ninu, awọn ileri Ọlọ́run ti n pa majẹmu mọ, Ẹni ti O ni eto rere fun ayé wa, gẹgẹ bi O ti ṣe fun Dafidi.

AṢARO LATI INU BÍBÉLÌ 

Mon. 15: OLUWA Fi Ami Ororo Yan Dafidi (O. D. 89:19-21)

Tue. 16: OLUWA Fun Dafidi Ni Ìṣẹgun (O. D. 89:22-23)

Wed. 17; OLUWA Fi Oore-Ọfẹ Han Fun Un (O. D. 89: 24-25)

Thur. 18: Majẹmu OLUWA Duro Pẹlu Dafidi (O. D. 89:26-29).

Fri. 19: Majẹmu Naa Tan De Ori Awọn Ọmọ Rẹ (O. D. 89: 30-32).

Sat. 20: OLUWA Ko Ni Mu Iṣeun Ifẹ Rẹ Kuro (O. D. 89:33)

ÀṢÀRÒ FUN ÌFỌKÀNSÌN 

1. Majẹmu Dafidi nṣafihan iṣeun ati iṣotitọ Ọlọ́run si awọn ti wọn și jẹ olootọ ati olufaraji si I.

2. Nigba ti a ba n gbe igbe aye títọ pẹlu ìṣẹ́ iriju ati awọn amuyẹ ìṣàkóso tòótọ́, Ọlọ́run jẹ́ olootọ lati ṣagbekalẹ májẹ̀mú Rẹ ati lati mu un ṣẹ pẹ̀lú wa.

ẸSẸ BIBELI FUN IPILẸ Ẹ̀KỌ́: 1Kronika 17:11-14

ILEPA ATI ÀWỌN ERONGBA

ILEPA: Lati sọ asoye nipa májẹ̀mú Ọlọ́run pẹlu Dafidi ti n ṣafihan Rẹ gẹgẹ bi Ọlọ́run majẹmu ati Olupa májẹ̀mú mọ.

ÀWỌN ERONGBA: Ni opin ẹ̀kọ́ yii, awọn akẹ́kọ̀ọ́ gbọ́dọ̀ le:

i. ṣàlàyé ohun ti majẹmu Dafidi jẹ;

ii. ṣafihan Ọlọ́run gẹgẹ bi Ọlọ́run ti n pa májẹ̀mú mọ ti O si jẹ olootọ; ati

iii. tọkasi awọn ọna lati wọnu májẹ̀mú ibaṣepo titi aye pẹlu Ọlọ́run. 

IFAARA

ORISUN Ẹ̀KỌ́: 2 SAMUELI 7:5-12; ORIN DAFIDI 89:3-4, 34-37; 132:11-12; ISE 2:22SWJ.
Ogo ni fun Ọlọ́run fun awọn ẹkọ ti O ti kọ wa ni awọn ọ̀sẹ̀ to ti kọjá lọ. Ni ọsẹ to kọjá yii, a wo: Ìjọba Israeli, nibi ti a ti kẹ́kọ̀ọ́ nipa iṣejọba awọn ọba Israeli ati agbekalẹ Ìjọba naa.

Ni ọsẹ yii, a o wo: Majẹmu Dafidi, eyi ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si awọn ìlérí Rẹ lati irandiran. A o ri bi Ọlọ́run ti ṣèlérí fun Dafidi pe ìjọba rẹ yoo maa wa titi nípasẹ̀ arọmọdọmọ rẹ, a si fi ìdánilójú diduro tiiri ati itẹsiwaju rẹ mulẹ. Majẹmu Laelae yii n tọkasi iṣotitọ ati ifaraji Ọlọ́run ti ki i yẹ si mimu awọn ileri Rẹ ṣẹ fun awọn ti wọn ba ṣi jẹ olootọ si I laiyẹsẹ.

Bi oni ti jẹ ọjọ awọn Baba ti ọdun 2026, a n ran wa leti nipa bi Ọlọ́run, Baba wa ọ̀run, ti jẹ olootọ nigba gbogbo ni titọju wa. Ẹ jẹ ki a kọ lati gbe ibaṣepọ to le koko pẹ̀lú Rẹ ro, ẹni ti yoo ba fi ogun ini titi lae silẹ fun awọn iran ọjọ ọla. A o bukun fun wa ni orúkọ Jesu. Amin.

KOKO EKO
I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸLU DÁFÍDÌ 

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DÁFÍDÌ 

ITUPALẸ Ẹ̀KỌ́ 

I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸ̀LÚ DAFIDI (2 Sam. 7:5-12; O. D. 89:3,4).

Nigba ti ọjọ rẹ ba pe, ti ìwọ o si sun pẹ̀lú awọn baba rẹ, Emi o si gbe iru ọmọ rẹ leke lẹ́yìn rẹ, eyi ti o ti inu rẹ jade wa, Emi o si fi idi ìjọba rẹ kalẹ (2 Sam. 7:12).

a. Ọlọ́run, ninu titobi ọlanla Rẹ jẹ Oluṣagbekalẹ májẹ̀mú ati Olùpa majẹmu mọ. Pẹlu pe O jẹ Aiku, O finnufindọ wọnu idipọ/àdéhùn pẹlu eniyan ti i ṣe ẹni kiku ati alaipe.

b. Ni Heberu, "beriyth" n tọkasi àdéhùn laarin ẹgbẹ́(ẹni) meji, nibi ti ẹgbẹ́ (ẹni) kọọkan ti ni lati faraji si pipa awọn ìlérí ti wọn ṣe mọ.

d. Òye niti majẹmu pẹ̀lú Ọlọ́run jẹ́ aarin gbungbun ninu Bibeli, o sin ṣafihan abuda ara ọtọ Rẹ. A gbọ́dọ̀ ni ilepa lati maa ṣafarawe abuda Ọlọ́run yii ninu aye ti wa naa

e. 2 Sam. 7:5-17: Ọlọ́run dá majẹmu ti ko ni tori ninu pẹlu Dafidi, yàtọ̀ si majẹmu Rẹ pẹlu Noa, Abrahamu ati Israẹli.

ẹ. O. D 89:3-4: Ọlọ́run ṣèlérí lati ṣagbekalẹ iru ọmọ Dafidi O si gbe itẹ rẹ ro titi laelae (1 Kron. 22:9-10; 28:5-6). Iru Ọlọ́run olotitọ wo ni a n sin yii!

f. Lati ni iriri majẹmu Ọlọ́run nitootọ, a gbọ́dọ̀ mu ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Rẹ ni pataki julọ, ki a gbe ibaṣepọ titi aye ro pẹlu Rẹ ki awọn ileri Rẹ le wa si ìmúṣẹ ninu aye wa. Ìṣẹ́ isin wa tootọ si Ọlọ́run yoo fi ipa rere lélẹ̀ eyi ti yoo maa fọhun síbẹ̀ lẹyin ti a ba lọ tan.

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DAFIDI (O. D. 89: 34-37; 132:11-12; Işe 2:22swj).

Nitori ti iṣe wolii, ati bi o ti mọ pe, Ọlọ́run ti fi ibura ṣe ileri fun un pe, Ninu iru ọmọ inu rẹ, oun o mu ọkan ìjókòó lori itẹ rẹ (Iṣe. 2:30)

a. O. D. 89:34: Ọlọ́run, Oludamajẹmu ati Olupa majẹmu mọ jẹ olootọ si awọn ileri Rẹ nigba gbogbo (Ìṣe 2:29-37). Eyi mu ki Bibeli ṣe e sinmile ti o si wa titi laelae.

b. Ila 34-37; Ọlọ́run n kiyesi awọn majẹmu Rẹ lati ri i daju pe a ṣe ìmúṣẹ wọn ni pipe. Àwọn ileri Rẹ jẹ ojulowo síbẹ̀, niwọn igba ti a ba ti jẹ olootọ si ojúṣe ti wa, bi o tilẹ̀ jẹ́ pe eniyan le kuna (132:11, 12).

d. 132:11-12: O bu ọla fun májẹ̀mú Rẹ pẹlu Dafidi nipa ṣiṣe agbekalẹ ila ìdílé reẹ gẹgẹ bi oluṣejọba Israeli ti o to fun gbogbo iran.

e. Ila 11: Ileri lati mu ila ìdílé Dafidi gẹgẹ bi ọba duro, níkẹyìn n tọkasi ìmúṣẹ ọjọ ọla ti ìṣejọba Mesaya, ti a muṣẹ ninu Kristi Jesu, Ọba awọn ọba (Ifi. 22:5).

ẹ. Ìṣe 2:22swj: Pétérù ṣàlàyé bi ajinde Jesu ti mu asọtẹlẹ Dafidi ṣẹ, pe, agọ̀ ara Mèsáyà ki yoo dibajẹ, eyi n ṣafihan isopọ laarin Dafidi ati Jesu (O. D 16:10).

f. Majẹmu Dafidi n ṣafihan ipa ara ọtọ Dafidi ninu itan Bibeli ati itẹsiwaju laarin Majẹmu Laelae ati Majẹmu Tuntun, ti o yọrisi ọdọ Jesu, Iru ọmọ Dafidi ti a ti ṣèlérí naa (Lk. 1:32).

AWỌN Ẹ̀KỌ́ TI A RI KỌ

1. Majẹmu Dafidi n ru awọn onigbagbọ sókè lati maa bọlá fun Ọlọ́run ki wọn si maa gbe ogun ini titi laelae ro.

2. Iṣotitọ Ọlọ́run n fun wa ni ẹmi irẹlẹ, o n ru wa sókè lati mọ títóbi julọ ìjọba Rẹ ati lati dagba nipa tẹmi.

ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

1. Ṣalaye iṣotitọ Ọlọ́run ati títóbi julọ Rẹ ninu majẹmu Dafidi. Awọn ẹkọ wo ni a le kọ lara eyi lonii?

2. Bawo ni awọn onigbagbọ ninu Kristi ṣe le mu majẹmu Ọlọ́run dúró lode lonii?

ÌDÁHÙN TI A DABAA FUN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

ÌDÁHÙN SI ÌBÉÈRÈ 1

* Ọlọ́run ninu titobi julọ Rẹ, yan Dafidi gẹ́gẹ́ bi ẹni ami ororo Rẹ O si da majẹmu àìnípẹ̀kun lati fidi ìjọba rẹ múlẹ̀. 

* Majẹmu yii ṣan wọnu majẹmu ti Mèsáyà pẹlu awọn ènìyàn Ọlọ́run. 

* Dafidi ò gba majẹmu yii nípasẹ̀ iwa òdodo rẹ; ìyàn Ọlọ́run, ti o da lori oore-ọfẹ Rẹ ni, kii ṣe mímọ-ọn-ṣe Dafidi.

* Ninu iṣotitọ Rẹ, Ọlọ́run ri i dájú pé majẹmu yii di mimúṣẹ (O. D. 89:34).

* Dafidi ko ipa pataki nipa gbigbe ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Ọlọ́run ro, ní bí o ti ṣàkóso pẹlu òtítọ́ inu, ọkan olùsọ-àgùntàn, ati iwa irẹlẹ to jinlẹ.

* Awon eko fun wa lonii:

        * Awọn obi gbọ́dọ̀ ko/gbe ogun ini oniwa-bi-Ọlọrun ro fun awọn ọmọ wọn.

        * Eyi n yanana pàtàkì ogun ini ìdílé ati ipa rẹ lori awọn iran ọjọ́ ọla.

IDAHUN SI IBEERE 2
A le pa majẹmu Ọlọ́run mọ laaye ninu aye wa lonii nipa:

i. Gbígbé ibaṣepọ to kun fun Ẹ̀mi ti o si le koko ro pẹlu Ọlọ́run;

ii. Ṣiṣe agbekalẹ akoko ìfọkànsìn ti ìdílé lojoojumọ;

iii. Kíkọ ìdílé rẹ ni awọn ẹkọ ati ilana Bibeli to ṣe iyebiye;

iv. Fifaaye gba Jesu lati dari ati lati maa tọ idile rẹ;

v. Fifi Jésù han ìdílé/ẹbi rẹ - Oun ni ẹ̀bùn ti o tobi julọ;

vi. Fifun Ọlọ́run ni ìjọsìn tòótọ́ ati eyi to ṣe itẹwọgba;

vii. Jijẹ ẹni to n kopa to si n ṣe deede ninu ìṣẹ́ isin Ọlọ́run pẹ̀lú awọn ọmọ rẹ;

viii. Ṣiṣatilẹyin ìṣe Ọlọ́run ninu ijọ ti o n lọ; ati

ix. Riri isẹra ẹni/ibawi gẹ́gẹ́ bi ami ifẹ Ọlọ́run ati ipongbẹ Rẹ lati ṣe odiwọn wa sinu àwòrán Rẹ.

ÀMÚLÒ FUN IGBE AYE ẸNI 

Ọlọ́run ni eto ara-ọ̀tọ̀ fun olukuluku wa, gẹgẹ bi O ti ni in fun eyi si bẹ̀rẹ̀ pẹlu gbígbẹkẹle E ati titẹle awọn àṣẹ Rẹ. A le ma fi igba gbogbo ni ẹkunrẹrẹ oye eto Rẹ, ṣugbọn a le ni ìdánilójú pe ọna Rẹ tayọ ohunkohun ti a le finuro. Ẹ jẹ ki a kọjú wasi gbigbe igbe aye to n bu ọlá fun Ọlọ́run ki a si kó ogun ini ti n ṣafihan ìfẹ́ ati iṣotitọ Rẹ. Gẹgẹ bi baba to mọ ikẹ ati igẹ ti maa n tọju awọn ọmọ rẹ, Ọlọ́run wa fun wa nigba gbogbo, On tọ wa pẹlu itọju ìfẹ́ Rẹ̀. Ẹ jẹ ki a maa gbe ayé wa ni ọna to ba ifẹ Rẹ mu, ki a gbẹkẹle E lati dari wa si ọjọ́ ọ̀la ti O ti ṣètò fun wa.

IGUNLẸ 
Eyi ni igunlẹ Ẹ̀kọ 22. A gba wa níyànjú lati faramọ majẹmu Ọlọ́run, ati gẹgẹ bi obi, oluṣo-aguntan ati olutọnisọna, a gbọ́dọ̀ lakaka lati gbe ogun ini oníwà-bí-Ọlọ́run ti yoo wa laelae ró, gẹgẹ bi ti majẹmu Dafidi. Awọn obi gbọ́dọ̀ maa gbadura fun ọjọ́ ọ̀la awọn ọmọ wọn, ki wọn maa ṣàfẹ́rí ìtọ́ni ati ìbùkún Ọlọ́run fun wọn.

ÀkíyèsíÌjọ Aposteli Kristi
Nàìjíríà Àti Òkè Òkun

ILÉ Ẹ̀KỌ́ ỌJỌ́ ÌSINMI

Akori Gbooro:
BÍBÉLÌ NÁÀ: ỌRỌ/ÌṢẸ ỌLỌ́RUN SI ÈNÌYÀN

Oṣù Kínní si oṣù Kejila 2026

Isọri III:
Àwọn Májẹ̀mú Ọlọ́run Àti Igbe Ayé Nínú Májẹ̀mú Láéláé 

June 21, 2026 

Ẹ̀KỌ́ 22

Akori:
Majẹmu Dafidi

Akọsórí:
Emi ti ba ayanfẹ mi da majẹmu, Emi ti bura fun Dafidi, ìránṣẹ́ Mi, iru ọmọ rẹ ni Emi o gbe kalẹ laelae, Emi o si maa gbe itẹ rẹ ro lati irandiran (Orin Dafidi 89:3,4).

Ọlọ́run ṣèlérí nipa itẹ Dafidi lati wa laelae, majẹmu titi aye fun irandiran, ogun-ini ti ìgbàgbọ́ ati ileri

ÀLÀYÉ KÚKÚRÚ 
Ninu Saamu yii, Onisaaamu yii n ronu nipa ìṣàkóso Ọlọ́run to ga julọ lori ohun gbogbo, o si n ran wa leti pe ko si ohun ti o N le ṣẹlẹ̀ laisi ìfẹ́ Rẹ̀. Bakan naa ni o tun n yọ si ileri Ọlọ́run fun Dafidi, ti o si sọ fun un pe iru ọmọ rẹ ni yoo maa jokoo lori itẹ naa nigba gbogbo. Nigba ti ileri yii bẹ̀rẹ̀ pẹlu ila Dafidi, ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìtumọ̀ rẹ jẹyọ níkẹyìn ninu ijọba Kristi, ti o wa lati inu idile Dafidi. Dafidi, Oluṣọ aguntan to nirẹlẹ, jẹ ẹni bi ọkan Ọlọ́run. O dari Israẹli pẹ̀lú iwa ododo ati òtítọ́ inu, ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si majẹmu Rẹ.

Ileri yii si Dafidi n ran wa leti pe Bibeli ki iṣe akojọpọ awọn itan kan lasan-ọrọ/iṣe Ọlọ́run ni si wa. On ṣe afihan abuda aiyipada ti Ọlọrun fun wa, pẹlu iṣotitọ Rẹ ati awọn ìlérí ti On pamọ ni gbogbo irandiran. Nigba ti a ba n ro nipa eyi, a n gba wa niyanju lati ni ìgbẹ́kẹ̀lé ninu, awọn ileri Ọlọ́run ti n pa majẹmu mọ, Ẹni ti O ni eto rere fun ayé wa, gẹgẹ bi O ti ṣe fun Dafidi.

AṢARO LATI INU BÍBÉLÌ 

Mon. 15: OLUWA Fi Ami Ororo Yan Dafidi (O. D. 89:19-21)

Tue. 16: OLUWA Fun Dafidi Ni Ìṣẹgun (O. D. 89:22-23)

Wed. 17; OLUWA Fi Oore-Ọfẹ Han Fun Un (O. D. 89: 24-25)

Thur. 18: Majẹmu OLUWA Duro Pẹlu Dafidi (O. D. 89:26-29).

Fri. 19: Majẹmu Naa Tan De Ori Awọn Ọmọ Rẹ (O. D. 89: 30-32).

Sat. 20: OLUWA Ko Ni Mu Iṣeun Ifẹ Rẹ Kuro (O. D. 89:33)

ÀṢÀRÒ FUN ÌFỌKÀNSÌN 

1. Majẹmu Dafidi nṣafihan iṣeun ati iṣotitọ Ọlọ́run si awọn ti wọn și jẹ olootọ ati olufaraji si I.

2. Nigba ti a ba n gbe igbe aye títọ pẹlu ìṣẹ́ iriju ati awọn amuyẹ ìṣàkóso tòótọ́, Ọlọ́run jẹ́ olootọ lati ṣagbekalẹ májẹ̀mú Rẹ ati lati mu un ṣẹ pẹ̀lú wa.

ẸSẸ BIBELI FUN IPILẸ Ẹ̀KỌ́: 1Kronika 17:11-14

ILEPA ATI ÀWỌN ERONGBA

ILEPA: Lati sọ asoye nipa májẹ̀mú Ọlọ́run pẹlu Dafidi ti n ṣafihan Rẹ gẹgẹ bi Ọlọ́run majẹmu ati Olupa májẹ̀mú mọ.

ÀWỌN ERONGBA: Ni opin ẹ̀kọ́ yii, awọn akẹ́kọ̀ọ́ gbọ́dọ̀ le:

i. ṣàlàyé ohun ti majẹmu Dafidi jẹ;

ii. ṣafihan Ọlọ́run gẹgẹ bi Ọlọ́run ti n pa májẹ̀mú mọ ti O si jẹ olootọ; ati

iii. tọkasi awọn ọna lati wọnu májẹ̀mú ibaṣepo titi aye pẹlu Ọlọ́run. 

IFAARA

ORISUN Ẹ̀KỌ́: 2 SAMUELI 7:5-12; ORIN DAFIDI 89:3-4, 34-37; 132:11-12; ISE 2:22SWJ.
Ogo ni fun Ọlọ́run fun awọn ẹkọ ti O ti kọ wa ni awọn ọ̀sẹ̀ to ti kọjá lọ. Ni ọsẹ to kọjá yii, a wo: Ìjọba Israeli, nibi ti a ti kẹ́kọ̀ọ́ nipa iṣejọba awọn ọba Israeli ati agbekalẹ Ìjọba naa.

Ni ọsẹ yii, a o wo: Majẹmu Dafidi, eyi ti n ṣafihan jíjẹ olootọ Ọlọ́run si awọn ìlérí Rẹ lati irandiran. A o ri bi Ọlọ́run ti ṣèlérí fun Dafidi pe ìjọba rẹ yoo maa wa titi nípasẹ̀ arọmọdọmọ rẹ, a si fi ìdánilójú diduro tiiri ati itẹsiwaju rẹ mulẹ. Majẹmu Laelae yii n tọkasi iṣotitọ ati ifaraji Ọlọ́run ti ki i yẹ si mimu awọn ileri Rẹ ṣẹ fun awọn ti wọn ba ṣi jẹ olootọ si I laiyẹsẹ.

Bi oni ti jẹ ọjọ awọn Baba ti ọdun 2026, a n ran wa leti nipa bi Ọlọ́run, Baba wa ọ̀run, ti jẹ olootọ nigba gbogbo ni titọju wa. Ẹ jẹ ki a kọ lati gbe ibaṣepọ to le koko pẹ̀lú Rẹ ro, ẹni ti yoo ba fi ogun ini titi lae silẹ fun awọn iran ọjọ ọla. A o bukun fun wa ni orúkọ Jesu. Amin.

KOKO EKO
I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸLU DÁFÍDÌ 

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DÁFÍDÌ 

ITUPALẸ Ẹ̀KỌ́ 

I. MAJẸMU AYÉRAYÉ ỌLỌ́RUN PẸ̀LÚ DAFIDI (2 Sam. 7:5-12; O. D. 89:3,4).

Nigba ti ọjọ rẹ ba pe, ti ìwọ o si sun pẹ̀lú awọn baba rẹ, Emi o si gbe iru ọmọ rẹ leke lẹ́yìn rẹ, eyi ti o ti inu rẹ jade wa, Emi o si fi idi ìjọba rẹ kalẹ (2 Sam. 7:12).

a. Ọlọ́run, ninu titobi ọlanla Rẹ jẹ Oluṣagbekalẹ májẹ̀mú ati Olùpa majẹmu mọ. Pẹlu pe O jẹ Aiku, O finnufindọ wọnu idipọ/àdéhùn pẹlu eniyan ti i ṣe ẹni kiku ati alaipe.

b. Ni Heberu, "beriyth" n tọkasi àdéhùn laarin ẹgbẹ́(ẹni) meji, nibi ti ẹgbẹ́ (ẹni) kọọkan ti ni lati faraji si pipa awọn ìlérí ti wọn ṣe mọ.

d. Òye niti majẹmu pẹ̀lú Ọlọ́run jẹ́ aarin gbungbun ninu Bibeli, o sin ṣafihan abuda ara ọtọ Rẹ. A gbọ́dọ̀ ni ilepa lati maa ṣafarawe abuda Ọlọ́run yii ninu aye ti wa naa

e. 2 Sam. 7:5-17: Ọlọ́run dá majẹmu ti ko ni tori ninu pẹlu Dafidi, yàtọ̀ si majẹmu Rẹ pẹlu Noa, Abrahamu ati Israẹli.

ẹ. O. D 89:3-4: Ọlọ́run ṣèlérí lati ṣagbekalẹ iru ọmọ Dafidi O si gbe itẹ rẹ ro titi laelae (1 Kron. 22:9-10; 28:5-6). Iru Ọlọ́run olotitọ wo ni a n sin yii!

f. Lati ni iriri majẹmu Ọlọ́run nitootọ, a gbọ́dọ̀ mu ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Rẹ ni pataki julọ, ki a gbe ibaṣepọ titi aye ro pẹlu Rẹ ki awọn ileri Rẹ le wa si ìmúṣẹ ninu aye wa. Ìṣẹ́ isin wa tootọ si Ọlọ́run yoo fi ipa rere lélẹ̀ eyi ti yoo maa fọhun síbẹ̀ lẹyin ti a ba lọ tan.

II. IṢOTITỌ ỌLỌ́RUN SI MAJẸMU DAFIDI (O. D. 89: 34-37; 132:11-12; Işe 2:22swj).

Nitori ti iṣe wolii, ati bi o ti mọ pe, Ọlọ́run ti fi ibura ṣe ileri fun un pe, Ninu iru ọmọ inu rẹ, oun o mu ọkan ìjókòó lori itẹ rẹ (Iṣe. 2:30)

a. O. D. 89:34: Ọlọ́run, Oludamajẹmu ati Olupa majẹmu mọ jẹ olootọ si awọn ileri Rẹ nigba gbogbo (Ìṣe 2:29-37). Eyi mu ki Bibeli ṣe e sinmile ti o si wa titi laelae.

b. Ila 34-37; Ọlọ́run n kiyesi awọn majẹmu Rẹ lati ri i daju pe a ṣe ìmúṣẹ wọn ni pipe. Àwọn ileri Rẹ jẹ ojulowo síbẹ̀, niwọn igba ti a ba ti jẹ olootọ si ojúṣe ti wa, bi o tilẹ̀ jẹ́ pe eniyan le kuna (132:11, 12).

d. 132:11-12: O bu ọla fun májẹ̀mú Rẹ pẹlu Dafidi nipa ṣiṣe agbekalẹ ila ìdílé reẹ gẹgẹ bi oluṣejọba Israeli ti o to fun gbogbo iran.

e. Ila 11: Ileri lati mu ila ìdílé Dafidi gẹgẹ bi ọba duro, níkẹyìn n tọkasi ìmúṣẹ ọjọ ọla ti ìṣejọba Mesaya, ti a muṣẹ ninu Kristi Jesu, Ọba awọn ọba (Ifi. 22:5).

ẹ. Ìṣe 2:22swj: Pétérù ṣàlàyé bi ajinde Jesu ti mu asọtẹlẹ Dafidi ṣẹ, pe, agọ̀ ara Mèsáyà ki yoo dibajẹ, eyi n ṣafihan isopọ laarin Dafidi ati Jesu (O. D 16:10).

f. Majẹmu Dafidi n ṣafihan ipa ara ọtọ Dafidi ninu itan Bibeli ati itẹsiwaju laarin Majẹmu Laelae ati Majẹmu Tuntun, ti o yọrisi ọdọ Jesu, Iru ọmọ Dafidi ti a ti ṣèlérí naa (Lk. 1:32).

AWỌN Ẹ̀KỌ́ TI A RI KỌ

1. Majẹmu Dafidi n ru awọn onigbagbọ sókè lati maa bọlá fun Ọlọ́run ki wọn si maa gbe ogun ini titi laelae ro.

2. Iṣotitọ Ọlọ́run n fun wa ni ẹmi irẹlẹ, o n ru wa sókè lati mọ títóbi julọ ìjọba Rẹ ati lati dagba nipa tẹmi.

ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

1. Ṣalaye iṣotitọ Ọlọ́run ati títóbi julọ Rẹ ninu majẹmu Dafidi. Awọn ẹkọ wo ni a le kọ lara eyi lonii?

2. Bawo ni awọn onigbagbọ ninu Kristi ṣe le mu majẹmu Ọlọ́run dúró lode lonii?

ÌDÁHÙN TI A DABAA FUN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ 

ÌDÁHÙN SI ÌBÉÈRÈ 1

* Ọlọ́run ninu titobi julọ Rẹ, yan Dafidi gẹ́gẹ́ bi ẹni ami ororo Rẹ O si da majẹmu àìnípẹ̀kun lati fidi ìjọba rẹ múlẹ̀. 

* Majẹmu yii ṣan wọnu majẹmu ti Mèsáyà pẹlu awọn ènìyàn Ọlọ́run. 

* Dafidi ò gba majẹmu yii nípasẹ̀ iwa òdodo rẹ; ìyàn Ọlọ́run, ti o da lori oore-ọfẹ Rẹ ni, kii ṣe mímọ-ọn-ṣe Dafidi.

* Ninu iṣotitọ Rẹ, Ọlọ́run ri i dájú pé majẹmu yii di mimúṣẹ (O. D. 89:34).

* Dafidi ko ipa pataki nipa gbigbe ibaṣepọ timọtimọ pẹlu Ọlọ́run ro, ní bí o ti ṣàkóso pẹlu òtítọ́ inu, ọkan olùsọ-àgùntàn, ati iwa irẹlẹ to jinlẹ.

* Awon eko fun wa lonii:

        * Awọn obi gbọ́dọ̀ ko/gbe ogun ini oniwa-bi-Ọlọrun ro fun awọn ọmọ wọn.

        * Eyi n yanana pàtàkì ogun ini ìdílé ati ipa rẹ lori awọn iran ọjọ́ ọla.

IDAHUN SI IBEERE 2
A le pa majẹmu Ọlọ́run mọ laaye ninu aye wa lonii nipa:

i. Gbígbé ibaṣepọ to kun fun Ẹ̀mi ti o si le koko ro pẹlu Ọlọ́run;

ii. Ṣiṣe agbekalẹ akoko ìfọkànsìn ti ìdílé lojoojumọ;

iii. Kíkọ ìdílé rẹ ni awọn ẹkọ ati ilana Bibeli to ṣe iyebiye;

iv. Fifaaye gba Jesu lati dari ati lati maa tọ idile rẹ;

v. Fifi Jésù han ìdílé/ẹbi rẹ - Oun ni ẹ̀bùn ti o tobi julọ;

vi. Fifun Ọlọ́run ni ìjọsìn tòótọ́ ati eyi to ṣe itẹwọgba;

vii. Jijẹ ẹni to n kopa to si n ṣe deede ninu ìṣẹ́ isin Ọlọ́run pẹ̀lú awọn ọmọ rẹ;

viii. Ṣiṣatilẹyin ìṣe Ọlọ́run ninu ijọ ti o n lọ; ati

ix. Riri isẹra ẹni/ibawi gẹ́gẹ́ bi ami ifẹ Ọlọ́run ati ipongbẹ Rẹ lati ṣe odiwọn wa sinu àwòrán Rẹ.

ÀMÚLÒ FUN IGBE AYE ẸNI 

Ọlọ́run ni eto ara-ọ̀tọ̀ fun olukuluku wa, gẹgẹ bi O ti ni in fun eyi si bẹ̀rẹ̀ pẹlu gbígbẹkẹle E ati titẹle awọn àṣẹ Rẹ. A le ma fi igba gbogbo ni ẹkunrẹrẹ oye eto Rẹ, ṣugbọn a le ni ìdánilójú pe ọna Rẹ tayọ ohunkohun ti a le finuro. Ẹ jẹ ki a kọjú wasi gbigbe igbe aye to n bu ọlá fun Ọlọ́run ki a si kó ogun ini ti n ṣafihan ìfẹ́ ati iṣotitọ Rẹ. Gẹgẹ bi baba to mọ ikẹ ati igẹ ti maa n tọju awọn ọmọ rẹ, Ọlọ́run wa fun wa nigba gbogbo, On tọ wa pẹlu itọju ìfẹ́ Rẹ̀. Ẹ jẹ ki a maa gbe ayé wa ni ọna to ba ifẹ Rẹ mu, ki a gbẹkẹle E lati dari wa si ọjọ́ ọ̀la ti O ti ṣètò fun wa.

IGUNLẸ 
Eyi ni igunlẹ Ẹ̀kọ 22. A gba wa níyànjú lati faramọ majẹmu Ọlọ́run, ati gẹgẹ bi obi, oluṣo-aguntan ati olutọnisọna, a gbọ́dọ̀ lakaka lati gbe ogun ini oníwà-bí-Ọlọ́run ti yoo wa laelae ró, gẹgẹ bi ti majẹmu Dafidi. Awọn obi gbọ́dọ̀ maa gbadura fun ọjọ́ ọ̀la awọn ọmọ wọn, ki wọn maa ṣàfẹ́rí ìtọ́ni ati ìbùkún Ọlọ́run fun wọn.

Àkíyèsí

Thursday, April 02, 2026

Easter greetings



* "If we say we have no sin, we are misleading ourselves and the truth is not in us"(1 John 1: 8-10 ; Romans 5: 12). We all need Jesus Christ's ransom sacrifice (John 3: 16 ; 1 Corinthians 15: 22). All students who get below 100% in an exam need to listen to the teacher's corrections. 

May we not be self-righteous (like the Pharisee of Luke 18: 9-14) or abuse God's grace to continue in deliberate sin (Hebrews 10: 26- 31). Happy Easter.

______________________________________________


* Balaam failed to curse the Israelites while they were in good standing with God (Numbers chapters 22 - 24). He later got them to sin and earn God's wrath (Numbers 25: 1-15 ; 31: 15-18 ; Revelation 2: 14). May we not fall into our enemies' trap through deliberate sin (Hebrews 10: 26- 31). Happy Easter. 


::::::::::::::::::::::::::::::

May God enable us to do His will, even when it is not easy to do so (Luke 22: 41,42).His laws are for our benefit in the long run (Isaiah 48:17 ; Hebrews 2:9).

 ____...========= ========= ====

 God's love surpasses all understanding. (Deuteronomy 29:29 ; 1 Peter 1:12). When Satan instigated people to kill Jesus Christ, he didn't know that the move will accomplish God's purpose for humanity (Genesis 3:15) .May all our dreams come true, regardless of Satanic opposition. 

 ____...========= ========= ====

 Christ's resurrection establishes our hopes and silences our fears. Death has lost its sting and victory (1 Corinthians 15: 55). May we endure to the end and be saved (Matthew 24:13),while also sharing the good news with other people (Acts 20:20).

Wednesday, March 11, 2026

MUCH ADO ABOUT ELECTRICITY BILLS


Most banks require their new customers to bring electricity bills to regularise their bank accounts (including those opened online). While the bills are easy to get from one's landlord, neighbour or friend, they don't say much about one's identity and current location. They only provide a guarantor (the person whose name appears on the bill) for the account. A tenant may move out tomorrow.

A PVC (permanent voter's card) is more useful in tracking people down. It reveals the person's full names and date of birth, which can be entered into the INEC CVR portal to reveal the person's current address and polling unit even if he has moved. It is easy for a wanted person to be picked up (with some help from people living near the polling unit). 

On the other hand, a wanted person who has moved after using his landlord's electricity bill cannot be tracked. It is the innocent former landlord who will be asked questions he can't answer. It is safer to offer your electricity bill to your fellow landlord (a permanent neighbour) who doesn't use electricity than to your own tenant ( who may move to an unknown destination later). More and more people are dumping the erratic electricity for generators and solar energy. 

Banks should, please, move with the times. 


Monday, March 09, 2026

Dry season notice

Clean and plentiful water is at : (a) the two taps on the wall between the houses of Baba Soldier and Mr Abayo; (b) the well under the cocoa tree across the road; (c) the borehole near the church.

Sunday, January 18, 2026

"Dear Lord and father of mankind "

Dear Lord and Father of mankind,
forgive our foolish ways!
Reclothe us in our rightful mind;
in purer lives Thy service find,
in deeper rev'rence, praise.

2 In simple trust like theirs who heard,
beside the Syrian sea,
the gracious calling of the Lord,
let us, like them, without a word
Rise up and follow Thee.

3 O Sabbath rest by Galilee!
O calm of hills above,
where Jesus knelt to share with Thee
the silence of eternity,
interpreted by love!

4 Drop Thy still dews of quietness,
till all our strivings cease;
take from our souls the strain and stress,
and let our ordered lives confess
the beauty of Thy peace.

5 Breathe through the heats of our desire
Thy coolness and Thy balm;
let sense be dumb, let flesh retire;
speak through the earthquake, wind and fire,
O still small voice of calm!

Monday, December 22, 2025

"Gbé Wiri" by Mákǎnjúọlá Adérìnkòmí





This play exposes the antics of pickpockets, bribe-takers  and other criminals, and how nemesis catches up with them eventually. 

THE CAST

OWÓNIKÓKÓ, ÌGBÀLAYÉ = leaders of the robbery gang. 

 ORÍYỌMÍ = the man robbed of his money at Ìdó. 

ỌMỌ́WÙMÍ = Oríyọmí's child.

UGOKÉŃKÉ, ŃJỌKÀ, ŃWỌ́KÀ, ÒKÉRÉKORÒ = other robbers who come to Ìdó and join Owónikókó's gang. Òkérékorò later becomes a government witness against  Owónikókó.

KỌ́BÙRÙ, SÁJẸ́ǸTÌ, KỌ́ŃSTÉBÙ = corporal, sergeant and constable respectively (policemen handling the case).

MỌ̀ŃMỌ̀ = an Hausa man who buys a radio set from Owónikókó.


ACT 1

SCENE 1 :  Ìgbàlayé visits Owónikókó at home. Both complain about the hard times. Owónikókó stopped his education at Primary 6 and Ìgbàlayé at JSS 2. Both qualifications are inadequate for gainful employment. Still, they observe that some people they know become rich without any formal education. They eventually decide to become pick-pockets robbing bus passengers. Ìgbàlayé explains, "We will rob passengers while struggling to enter buses during rush hours and then get down to meet elsewhere to share the loot. Whoever hasn't robbed anyone can travel with the bus and get down before the conductors asks for money."

SCENE 2  :  Ìgbàlayé and Owónikókó arrive Tinubu Square at 3 pm with sharp blades to cut people's pockets. While at the bus door, Ìgbàlayé cuts someone's pocket, picks 10 naira and gets down for his "inability to get in". Owónikókó gets  ₦50 out of another passenger before leaping down from the bus. Ìgbàlayé's victim is unable to pay his transport fare. The two crooks meet and share the loot equally (at ₦30 each). They then enter a restaurant, where Owónikókó steals the seller's purse after asking for water to wash his face. Ìgbàlayé goes to Bristol Hotel while Owónikókó goes home.

SCENE 3:  Owónikókó visits Ìgbàlayé (who spent ₦20 at the hotel the previous day before a prostitute stole his remaining ₦10). Owónikókó suggests they work as luggage carriers at motor parks to camouflage their real intentions. They can make money legitimately as carriers, run away with people's luggages or pick passengers' pockets. They will thus have 3 avenues of making money. They can also help drivers and motor park touts to get passengers.  At an eatery in Ìdó, they meet a herbalist named Jẹ́jẹ́lékòó, who gives them free charms for detecting people with money on them but demands ₦150 for the charm that will make them invisible while stealing. 

:::::::::::::::: ACT 2  ::::::::::::::

SCENE 1  : Owónikókó escapes with a new bride's luggage at Ìdó motor park. He sells the contents for ₦500 and deposits ₦400 at Barclay's Bank (now First Bank). After filling a bus with passengers, they give the chief tout the transport fare and collect the change to give the passengers. In the process, Owónikókó picks ₦12 from the chief tout's side pocket. 

SCENE 2:  While Ìgbàlayé is waiting for an official period to rob people, Owónikókó tells him how he robbed the chief tout. Ẹsẹ̀gìrì (Owónikókó's greedy friend) and Arírebánijẹ follow the two to Mainland Hotel to eat. While Ẹsẹ̀gìrì thanks Owónikókó and Ìgbàlayé after the meal, Arírebánijẹ just departs. 

SCENE 3:  Owónikókó and Ìgbàlayé meet new friends at Ìdó. They are Ńwọ́kà, Ńjọkà, Ugokéńké and Òkérékorò and are all from the South East of the country. They tell Owónikókó and Ìgbàlayé that they don't need any coaching before starting work, as experienced thieves. They only need to learn Yoruba language, instead of speaking Pidgin English only. The rule is for each robber to hand over half his loot for the others to share. That same day, Òkérékorò picks ₦10 from a passenger while Ńjọkà picks ₦50. 

::::::::::::::  ACT 3 ::::::::::::::::

SCENE 1:    All the gang members meet at Ìdó motor park as usual. A private car owner drives towards them and they flock round him. Òkérékorò shouts, "There is fire under your vehicle". As Oríyọmí gets down to check his vehicle but sees no fire, Owónikókó tells him to open his car's bonnet. As he opens the bonnet with both hands, Owónikókó picks ₦60 from his pocket and runs away. Ọmọ́wùmí (Oríyọmí's child) catches Òkérékorò picking his own pocket and recovers his own ₦1 from him with a hot slap. The rogues run away before Oríyọmí discovers he has been robbed. All the ₦60 he withdrew from the bank that morning has disappeared. Oríyọmí and Ọmọ́wùmí park their car in a hidden place and trace the robbers. They find Òkérékorò alone and he rightly denies stealing from Oríyọmí. The motor park tout secretary promises to get the whole truth out of Òkérékorò and tells Oríyọmí to come back the next day. Ọmọ́wùmí has to go back to Ibadan without his school fees and beg the school authorities to be patient.  

SCENE 2:  The next day, Oríyọmí returns to the motor park where the tout secretary tells him, "Òkérékorò keeps denying stealing your money but promises to help you catch the thief, Owónikókó. He is not here currently but will come by tomorrow morning. Òkérékorò and I will track him down and either recover your money or get him arrested". When they meet the following morning, Owónikókó comes to the park with a brand new radio set and refuses to share any of the loot with Òkérékorò. He claims to be broke after using his loot to buy the radio.

SCENE 3:  Oríyọmí comes to the motor park to see the secretary after closing from work. The secretary tells Òkérékorò to take Oríyọmí to Owónikókó's house to recover the radio as evidence to present to the police. They hear the sound of a radio playing from the house of an Hausa man, Mọ̀ńmọ̀, who can't communicate with them because he can speak very little Yoruba and bought it from Owónikókó (as revealed by a neighbour). The neighbour (Mr Òtítọ́jù) also reveals that Owónikókó is of no fixed address and is a criminal. The secretary persuades Òkérékorò to follow Oríyọmí to the police station to report the case, assuring him he will be made a prosecution witness.   


::::::::::::::::  ACT 4 ::::::::::::::

SCENE 1:  While they are reporting to the police, Kọ́bùrù identifies Òkérékorò as a regular visitor to the police station for theft cases.  When Oríyọmí says he is literate enough to write his own statement and that he is educated beyond School Cert level, Kọ́bùrù reveals that the Inspector-general of Police has only a School Cert.  Kọ́bùrù helps Òkérékorò to write his own dictated statement. Oríyọmí is asked to come back the next day. Òkérékorò takes Kọ́bùrù to the Hausa man's house. When Kọ́bùrù tries to recover the radio, Mọ̀ńmọ̀ shows him the receipt he got from Owónikókó after buying the radio at₦48. Kọ́bùrù commends his honesty but Mọ̀ńmọ̀ refuses to give up the radio (even brandishing a knife) until Kọ́bùrù brings out his police ID card and explains things further. He then gives up both the radio and its receipt. 

SCENE 2:  Òkérékorò helps Kọ́bùrù to identify Owónikókó at the motor park at 5 am the next day. Owónikókó refuses to answer Kọ́bùrù's questions, resists arrest (even after seeing Kọ́bùrù's ID card) and brings out a knife (forcing Kọ́bùrù to bring out his own gun). He even tries to bribe Kọ́bùrù, who eventually manages to get him to the police station. Kọ́bùrù now reads the charges (about the March 20 robbery of Oríyọmí and his buying a radio set with the loot and then selling it). He denies knowing the radio set's owner even when confronted with the receipt. He is detained. The motor park secretary tells Oríyọmí about Owónikókó's arrest. 

SCENE 3:    Owónikókó denies ever having seen Oríyọmí before and says God will judge him for wrongly accusing him of theft. He eventually owns up when confronted with the radio again. Kọ́bùrù tells Oríyọmí to come back to the police station on March 30, when Owónikókó will be arraigned at the court on Mosáfẹ́jọ́  Road. Kọ́bùrù asks Oríyọmí for money to give Sájẹ́ǹtì (Sergeant) in addition to extending Oríyọmí's greetings. Oríyọmí refuses and leaves the station disappointed about the extortion attempt. The motor park secretary too expects a "reward" and asks how much he has given the police. Oríyọmí replies, "How can I be bribing people when I'm innocent and after I have been robbed? After the case has been completely settled, I can give gifts in appreciation". 

:::::::::::::: ACT 5 ::::::::::::::::

SCENE 1: On the said 30 March, the criminal is taken to court but the police prosecutor says, "The investigations are yet to be concluded". The case is postponed to 7 April and Owónikókó returned to police custody. Kọ́bùrù (Corporal Bọ́lájókòó) says the police prosecutor dislikes him personally. On April 7, the police prosecutor asks for 2 more weeks because "the policeman in charge of this case has gone to a higher court over another case today". This case is postponed to April 21. On April 21, Kọ́bùrù admits that his April 7 absence was due to the very reasons the prosecutor gave. Police protocol demands going to the higher court when 2 cases clash. After Oríyọmí has confirmed from the court clerk that his case is the first for the day, the police prosecutor has it moved to the tenth position! Kọ́bùrù now reveals, "Maybe the prosecutor thinks I have collected a bribe from you without sharing it with him". Oríyọmí goes to the judge's chambers to complain about the constant postponements, which affects his job as a teacher. The judge fixes the case for the very next Saturday, April 26 as the first case. 

SCENE 2:   On April 26, the case is heard. The judge ridicules Owónikókó for trying to intimidate him with cultist signals and then influence him with a letter (probably from bigwigs). Owónikókó claims to be working with the Nigeria Ports Authority but cites the wrong address and boss for the agency. When asked his mission at the motor park where he was caught, he  claims to be working part-time as a motor park tout. Oríyọmí's court statement mentions Òkérékorò as the person who saw Owónikókó pick his pocket. The case is postponed to May 3 for Òkérékorò to appear in court. 

SCENE 3:  Oríyọmí's other witness, Ugokéńké, can't appear in court because he has been sentenced to jail by that very court for another robbery the previous day. Òkérékorò appears and testifies truthfully (citing Owónikókó's confession of using Oríyọmí's money to buy the radio set). Owónikókó is sentenced to 9 months in prison because he has already spent 3 months in police custody. He is taken to Kirikiri Maximum Security Prison in Apapa. 

In addition, the judge decrees that : (a) the police around Ìdó should get a list of registered motor park touts from their association's chairman and secretary; (b) the police should arraign all the unregistered park touts ; (c) the motor park tout association in Ìdó should be disbanded forever because of their extortion of passengers and drivers; (d) each driver should call his own passengers himself. Defaulters who are arraigned will be jailed for 6 months or pay 500 naira fine. The court crowd jubilate on the new lease of life in motor parks. 

THE END. 





Ìjọ Aposteli Kristi Nàìjíríà Àti Òkè Òkun ILÉ Ẹ̀KỌ́ ỌJỌ́ ÌSINMI Akori Gbooro: BÍBÉLÌ NÁÀ: ỌRỌ/ÌṢẸ ỌLỌ́...